BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ojude Ọba 2019: Àwọn èèkàn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti péjú fún ayẹyẹ ojúde Ọba
Àkọlé àwòrán,
Ojude Oba tí ọdún yìí ti gbéra sọ pẹ̀lú oníruuru àwọn aṣọ alárànbara yorùba to ń wúni lóri, Awọn ẹgbẹ́ Tobalàṣẹ obinrin rèé nínú àṣọ okè aláwọ̀ ewé
Published
13 Ògún 2019
'Kò sí ohun tó burú nínú bí Ajimobi ṣe dá Yewande tó pa ọkọ rẹ̀ sílẹ̀'
Àwọn Fadá mẹ́rin gbà itusílẹ̀ lọwọ àwọn ajínigbé
Samuel Okwaraji: Ó pé ọgbọ̀n ọdún tí lónìí ti akọni àgbábọ̀ọ̀lù papo dà
Ẹ ṣe àwárí ọdànran tó bọ mọ́ọ yín lọ́wọ́ - Turkur Buratai
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Gbobaniyi lókùnrin àti lóbìrin ló ti lọ ki ọba aláde lóri ìjòkò
Àkọlé àwòrán,
Lẹ́gbẹ́ lẹ́gbẹ́ ni gbogbo àwọn ti wọ́n péju síbi ayéyé Ojude Oba tí ọdún 2019
Àkọlé àwòrán,
Tokùnrin tobinrin ló wọsọ ìgbà níbi àyẹyẹ ojude oba tọdún yìí, Ẹgbẹ́ Bọbakẹ́yẹ Ọkunrin ni àwọn yìí
Àkọlé àwòrán,
Tarúgbó tomidàn ló wà nibi àyẹyẹ yìí, gbogbo oju wọ́n lo gúrégé pèlú, àwọn ẹgbẹ́ bọ́bakẹ́yẹ obinrin rèé
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn olóyè àti èèkàn ìlú ló péjú
Àkọlé àwòrán,
Kìí ṣe àwọn ẹgbẹ́ gbẹ́ jọdá nìkàn ló péju, àwọn ọdọ náà jáde wá láti yẹ́ àṣ]a ìbílẹ̀ sí
Àkọlé àwòrán,
Aláàfin Ọyọ, ikú bábá yèyé, Ọba Lamidi Adeyemi náà péjú síbi ayẹyẹ ojúde Oba ní'lú Ijebu
Àkọlé àwòrán,
Gómínà ìpínlẹ̀ Ogun, Dapo Abiodun àti Awùjalẹ̀ Ijẹ̀bú Ọba Sikiru Adetona
Àkọlé àwòrán,
Gómìnà tẹ́lẹ̀rí ní ìpínlẹ̀ Ogun, Ọtunba Gbẹnga Daniels
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Bọ́baguntẹ ilẹ̀ Ijẹbu
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo ojú tó ti ríra típẹ tún ni àànfàni láti ṣe "Ẹ k;u àti"
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Obafunwaji Obinrin Adedoyin rèé nínú aṣọ ofi aláwọ̀ búlù
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Tobalaṣẹ Ọkunrin náà ko gbẹ́yìn
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Gbobaniyi lókùnrin àti lóbìrin ló ti lọ ki ọba aláde lóri ìjòkò
Fo Móríwú kọjá kí o tẹ̀síwájú
Móríwú
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ
04:37
Fídíò,
Mo gun alùpùpù fún ọjọ́ mẹ́ẹ̀dọ́gbọ̀n láti London dé Nàíjíríà láti kówójọ fún ìgbógunti àìsàn Polio - Okedeyi
, Duration 4,37
05:04
Fídíò,
"Bàbá mi ti fẹ́ mú ọjọ́ ìgbeyàwó mi, kí wọn tó dú u lọ́rùn sínú oko, à ṣe ẹni ẹlẹ́ni ní yóò gba ìṣe rẹ̀ ṣe"
, Duration 5,04
04:42
Fídíò,
Níbo Layé Kọjú Sí? Ṣé kí lọ́kọláya máa gbé ní ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ le mú ewu dání bí?
, Duration 4,42
01:36
Fídíò,
Àwọn ohun tí o lè ṣe rèé láti mú kí ọmọ rẹ má a jẹ èso àti ewébẹ̀ dáadáa
, Duration 1,36
02:21
Fídíò,
'Kò síná, kò sómi, àfi bí pé ìhòhò la wa ni, ọmọ ọdún méje kò fojú rínà ọba rí nílùú yìí'
, Duration 2,21
04:40
Fídíò,
Bí mo ṣe kọ́kọ́ rí àwòrán ọkọ mi lára àwọn tí wọ́n tú sílẹ̀ ní Ogbomoso mo ṣubú mo ń sun ẹkún ni - Ìyàwó ọ̀kan lára àwọn olùkọ́ tí wọ́n jí gbé
, Duration 4,40
01:20
Fídíò,
Yàtọ̀ sí oyún ìbejì,mọ̀ nípa bí obìnrin ṣe lè lóyún méjì ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ nínú kan ṣoṣo
, Duration 1,20
04:55
Fídíò,
Olùkọ́ tó ní ìpèníjà ojú kàwé gboyè Ọ̀mọ̀wé ní fásitì, ó ní ó wu òun láti jẹ́ amòfin, máa jà fún ọmọnìyàn
, Duration 4,55
04:20
Fídíò,
Oyún ọmọ mi kejì kò tíì pé oṣù mẹ́ta, tí mo fi kan ìdààmú nínú ìgbéyàwó, mo sun ṣégè ẹkún - Wasila Coded
, Duration 4,20
02:52
Fídíò,
"Ẹ má fi ìmọ̀ ẹ̀rọ ìtàkùn àgbàyé Tech wé Yahoo, èdé Yorùbá tí mo fí ń kọ́ ọ̀pọ̀ èèyàn ń mú kí owó wọlé fún wọn"
, Duration 2,52
01:23
Fídíò,
Ìdí tí wíwọ ṣòkòtò àwọ̀tẹ́lẹ̀ péńpé 'boxer' sún kò fi dára tó fún ọ
, Duration 1,23
05:31
Fídíò,
Ìbọn tí wọ́n yìn sí ọkọ mi kò ràn án, ìgbà tí wọ́n gba àpò ọwọ́ rẹ̀ ni ìbọn tó ràn án – ìyàwó ọmọ ẹgbẹ́ Accord tí wọ́n pa l'Esa Oke ṣalàyé
, Duration 5,31
04:07
Fídíò,
Ìkà kọ́ lọmọ ejò, àwa èèyàn là ń kó tiwa bá wọn- Taiwo Okikiola-Ọmọ elejo
, Duration 4,07
00:51
Fídíò,
Àǹfààní márùn-ún tó wà nínú kí obìnrin sùn láì wọ pátá
, Duration 0,51
Ìparí Móríwú
Ìròyìn tó ṣe kókó
Mi ò lérò pé mo lè dé ipò Ìmáàmù ìlú Ilorin, àmọ́, mo ti máa ń rí àwọn àpẹẹrẹ kan tipẹ́ - Ìmáàmù Ilorin tuntun
wákàtí kan sẹ́yìn
Mo Bimpe lérí láti gbé àwọn tó ní Lateef Adedimeji kọ́ ni bàbá àwọn ọmọ rẹ̀ lọ sílé ẹjọ́
wákàtí 4 sẹ́yìn
Ìbanilórúkọjẹ́ lẹ̀sùn ìkówójẹ tí wọ́n fi kàn mí, Oluomo sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tílé aṣòfin Ogun fagilé ẹ̀sùn tí wọ́n fi kan adarí ilé tẹ́lẹ̀
wákàtí 3 sẹ́yìn
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Báyìí ni ikọ̀ aláàbò Iru Ekùn ṣe ń mu àdínkù ba ìjínigbé àti ètò ààbò tó mẹ́hẹ nílẹ̀ Yorùbá pẹ̀lú ọmọ ẹgbẹ́ tó lé ní 80,000 - Sunday Igboho
21 Agẹmo 2026
Wo àwọn nǹkan tí Andy Burnham, Olóòtú ìjọba UK tuntun lóun yóò ṣe fún ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì
20 Agẹmo 2026
Iyabo Obasanjo àti olùdíje sípò gómìnà lẹ́gbẹ́ APC l‘Ogun, Yayi, ń tutọ́ síra wọn lójú
21 Agẹmo 2026
Àwọn oníjìbìtì orí ayélujára tọwọ́ bọ ojú òpó Ààrẹ Kenya, wọ́n ń bèèrè $320,000
18 Agẹmo 2026
Afurasí tíṣà tí wọ́n ló lu akẹ́kọ̀ọ́ pa jọ̀wọ́ ara rẹ̀ fún ọlọ̀pàá
19 Agẹmo 2026
Àṣìta ìbọn agbésùnmọ̀mí pa àwọn akẹ́kọ̀ọ́ lásìkò táwọn ológun ń dènà ìjínigbé
19 Agẹmo 2026
Àdó olóró Iran ṣekúpa ọmọ ogún Amẹ́ríkà méjì, ìkọlù bẹ̀rẹ̀ lákọ̀tun
19 Agẹmo 2026
Ẹgbẹ́ àwọn Kristẹni tako òfin tó sọ ọ́ di èèwọ̀ láti máa wàásù nínú ọkọ̀ akérò
19 Agẹmo 2026
Ìdí rèé tí ìgbéyàwó èmi àti Ayinla Kollington ṣe forí ṣánpọ́n - Salawa Abeni ṣàlàyé
20 Agẹmo 2026
Ìròyìn tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn jùlọ
1
Mo Bimpe lérí láti gbé àwọn tó ní Lateef Adedimeji kọ́ ni bàbá àwọn ọmọ rẹ̀ lọ sílé ẹjọ́
2
Adeleke gbẹ́sẹ̀ lé ẹgbẹ́ awakọ̀ èrò l‘Osun, pàṣẹ fún ọlọ́pàá láti ṣoro fún ẹni tó bá tàpá ṣófin
3
Ìdí rèé tí ìgbéyàwó èmi àti Ayinla Kollington ṣe forí ṣánpọ́n - Salawa Abeni ṣàlàyé
4
Obasanjo àti Osoba sọ òkò ọ̀rọ̀ síra wọn lórí ìbò 2003, àṣírí ọ̀pọ̀ ìpàdé ìdákọ́ńkọ́ tú àti ìdí táwọn gómínà AD ṣe pàdánù sọ́wọ́ PDP
5
Wo àwọn àyípadà tó máa wáyé sí ètò ààbò bí Ààrẹ Tinubu ṣe buwọ́lu àfikún ẹkùn iléeṣẹ́ ológun di méjìlá
6
Ìbanilórúkọjẹ́ lẹ̀sùn ìkówójẹ tí wọ́n fi kàn mí, Oluomo sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tílé aṣòfin Ogun fagilé ẹ̀sùn tí wọ́n fi kan adarí ilé tẹ́lẹ̀
7
APC àti Makinde ju òkò ọ̀rọ̀ lu ara wọn lórí ìdájọ́ ilé ẹjọ́ láti dènà EFCC láti ṣe ìwádìí ìṣúná Oyo
8
Ilé ẹjọ́ gba onídùúró Blessing CEO pẹ̀lu ₦20m lórí ẹ̀sùn jìbìtì ₦69.15m
9
Aláànú kan kéde láti ṣe alágbàtọ́ láéláé fún ọmọ mẹ́ta tí John Olaleye bí, olùkọ́ táwọn ajínigbé pa ní Oriire
10
Nǹkan mẹ́wàá ni mo ní àfojúsùn láti mójútó tí mo bá di gómìnà Osun - Najeem Salaam