BBC News, Yorùbá - Ìròyìn
Ìròyìn tó ṣe kókó
Obasanjo àti Osoba sọ òkò ọ̀rọ̀ síra wọn lórí ìbò 2003, àṣírí ọ̀pọ̀ ìpàdé ìdákọ́ńkọ́ tú àti ìdí táwọn gómínà AD ṣe pàdánù sọ́wọ́ PDP
Ni ọdun 2018 ni Osoba ninu atẹjade kan ti sọ pe Obasanjo ṣe ẹtanjẹ fun gbogbo awọn gomina to wa labẹ ẹgbẹ oṣelu AD ni ẹkun guusu iwọ oorun Naijiria eyi to mu ki awọn padanu ipo awọn ninu idibo naa.
Ẹ̀yin agbébọn, Iru Ekun ti bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ láwọn igbó tó wà lẹ́kùn Gúúṣù Kwara, ẹ tètè para mọ́, gbogbo ìlẹ̀ Ìgbómìnà ni máà dé - Sunday Igboho
BBC News Yoruba bawọn peju sibi eto naa to bẹrẹ ni nnkan bi ago meji abọ Ọsan, tawọn eeyan ẹkun Gusu Kwara si peju si lọpọ yanturu.
Ìwádìí BBC rèé lórí ẹ̀sùn àjẹbánu ₦44m táwọn aṣòfin Ondo fi kan Olórí ilé tí wọ́n fi ni kó fipò sílẹ̀
Awọn aṣofin naa fun olori ile aṣofin ti i ṣe Abẹnugan wọn; Olamide Oladiji,ni gbedeke di ọjọ Aiku, ọjọ Kẹrindinlọgbọn, oṣu Keje, ọdun 2026 lati kọwe fipo rẹ silẹ bibẹẹkọ awọn maa yọ nipo.
Ilé ìgbìmọ̀ Aṣojú-ṣòfin buwọ́lu àbádòfin fún ìdásílẹ̀ ọlọ̀pàá ìpínlẹ̀ lórílẹ̀èdè Nàìjíríà
Eyi waye l'Ọjọbọ, ọjọ kẹtalelogun oṣu Keje ọdun 2026 yii.
Wo ìdí tí Trump ṣe kọ lẹ́tà, kan sáárá sí Tinubu lórí gbígbógun ti ìgbéṣúmọ̀mí
Agbẹnusọ Tinubu, Bayo Onanuga ninu atẹjade kan to fi soju opo X rẹ ni Trump kan saara si Tinubu lorukọ awọn ọmọ Naijiria.
Bí iléẹjọ́ ṣe dá EFCC lọ́wọ́ kọ́ láti ṣe ìwádìí ìṣúná gómìnà Oyo, ẹgbẹ́ APM ní ẹ̀rù Makinde ló ń ba Tinubu
EFCC lo gbe akanṣe iwadii dide lati ṣe agbeyẹwo awọn owo iṣẹ akanṣe ti ijọba ipinlẹ Oyo gbe jáde.
Orin, Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́, Duration 1,01
Àkójọpọ̀ ìròyìn káàkiri àgbáyé tí kò ṣe è má gbọ̀ ọ́
Fídíò, Wo ewu tó wà nínú kí èèyàn máa fi ẹsẹ̀ lásán rìn tàbí gbé bàtà tí o bá wọ́ jáde, wọnú ilé padà , Duration 2,35
BBC News Yorubá tọpinpin ọ̀pọ̀ ewu tó wà nínú kí èèyàn máa fi ẹsẹ̀ lásán rìn tàbí gbé bàtà tí o bá wọ́ jáde, wọnú ilé padà.
Fídíò, Ohun tí BBC rí rèé níbùdó tí wọn ti ń po kẹ́míkà pọ̀ lọ́nà àìtọ̀ tó tó $400m táwọn ọmọ ilẹ̀ Mexico ń ṣe, Duration 1,46
Iléeṣẹ́ BBC lọ sí ibùdó tí wọn ti ń po kẹ́míkà pọ̀ lọ́nà àìtọ̀ èyí tó tó ₦400m táwọn ọmọ ilẹ̀ Mexico ń ṣe, ẹ wa wo ọ̀pọ̀ ohun àwòdamiẹnu tí a rí níbẹ̀.
Aláànú kan kéde láti ṣe alágbàtọ́ láéláé fún ọmọ mẹ́ta tí John Olaleye bí, olùkọ́ táwọn ajínigbé pa ní Oriire
Dokita Kunle Adegbite kede wi pe nipasẹ ajọ alaanu Twindad Foundation loun yoo fi ṣe alagbatọ awọn ọmọ mẹta naa ti orukọ wọn n jẹ Daniel, Joy ati Morayo Olalere.
BBC News Yorùbá ti wà lórí ìkànnì WhatsApp
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ
Ìròyìn Àkàgbádùn
ICPC ṣàwárí ayédèrú òṣìṣẹ́ 908 láwọn iléeṣẹ́ ìjọba Nàìjíríà àádọ́ta, ọlọ́pàá pọ̀ nínú wọn
Alaga ICPC, Musa Adamu Aliyu (SAN) fidi eyi mulẹ fun BBC.
Àtakò dìde lórí àlàyé ikú tó pa ọ́gágun Sani Abacha tó gba orí ayélujára, àlàyé rèé
Latigba ti iku Ọgagun Abacha ti jade sita, ni airyanjiyan ti wa kaakiri agbaye, paapaa nilẹ Naijiria to ti jẹ adari, ti awọn eeyan ko si gbagbe titi di asiko yii.
Kí ni ipa tí ìdásílẹ̀ ibùdó ológun tuntun ní Omu-Aran, Kwara, yóò ní lórí àwọn ajínigbé, àgbésùnmọ̀mí àti aráàlú? Àwọn onímọ̀ sọ̀rọ̀
Atẹjade kan ti Gomina ipinlẹ Kwara, Abdulrahman Abdulrasaq fi soju opo X rẹ lọjọ Iṣẹgun, ọjọ Kọkanlelogun, oṣu Keje sọ pe ilu Omu-Aran ni ijọba ibilẹ Irepodun ni ibudo ọmọ ogun naa maa wa.
Ọkùnrin tó gbé aláìsàn wá sílé ìwòsàn Adeoyo n'Ibadan yarí pé kò sí dókítà lẹ́nu iṣẹ́, ó yájú sí Nọ́ọ̀sì, ẹgbẹ́ àwọn Nọ́ọ̀sì fọnmú
Loju ẹsẹ ti wọn sọ fun ọkunrin naa pe ko si dokita lẹnu iṣẹ ni alẹ ọjọ naa, lo ti sọ ọrọ ọhun di ariwo, to si bẹrẹ sii ṣe ikọlu si nọọsi to ba lẹnu iṣẹ.
Wo ohun tó ń fà àìsàn rọpárọsẹ̀, ìtọ́jú àti ìdènà rẹ̀, báwọn èèyàn ṣe ń ní àìsàn náà láàrin ìṣẹ́jú kọ̀ọ̀kan ní Naijiria
Lónìí àyájọ́ ìlera ọpọlọ, BBC News Yorùbá bá dókítà oníṣègùn òyìnbó sọ̀rọ̀ láti mọ ohun tó ń fa àìsàn rọlápá-rọlẹ́sẹ̀ tí a mọ̀ sí Stroke, àwọn àmì rẹ̀, ìtọ́jú àti ìdènà rẹ̀.
Wo gbogbo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa WAFCON 2026
WAFCON ọdun yii yoo bẹrẹ lọjọ Aiku, ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu Keje ọdun 2026.
Ọlọ́pàá mẹ́rin tó gbégi dínà lójú pópó fi tipá gba rìbá N57,000 lọ́wọ́ ọ̀gá àjọ tó ń gbógun tìwà àjẹbánu, ICPC, ọ̀rọ̀ bẹ́yìn yọ
Lasiko yii, alaga ajọ to n gbogun ti iwa jibiti ati ajẹbanu nilẹ Naijiria, ICPC, Musa Aliyu ni awọn ọlọpaa kan fọwọ ṣikun ofin gbe nilu Abuja, ti wọn si fi ẹsun titapa si ofin kan an, leyi to jẹ ki wọn beere owo lọwọ rẹ.
CBN kéde ẹni tó pàṣẹ pé kí wọn ṣí àkáǹtì fún ayédèrú iléeṣẹ́ PFIPC lábẹ́ Adeniyi Adeyemi, bí Gbajabiamila ṣe ń rojọ́ níwájú àjọ ICPC
Femi Gbajabiamila farahan niwaju ajọ ICPC lẹyin ti Aarẹ Bola Tinubu paṣẹ pe ki ajọ naa ṣe iwadii finifini lori ọrọ naa.
Oluwo dá ẹgbẹ́ lọ́balọ́ba lẹ́kùn ìdìbò Ìwọ̀ oòrùn Osun sílẹ̀, di alága láéláé, àwọn ọba míì fi èrò wọn hàn
Oluwo ni awọn ọba to wa ni ẹkun iwọ oorun Osun ni wọn woye pe o yẹ ki iṣọkan wa laaarin gbogbo wọn, ti wọn si da labaa lati da igbimọ naa silẹ.
Wo àwọn nǹkan mẹ́fà tó ti yípadà lẹ́yìn ìdìbò 2023 tó le nípa lórí ìdìbò 2027
Ọdun mẹrin mii tun ti de tawọn eeyan yoo tun maa dibo pẹlu gbogbo ayipada to ti waye lẹka oṣelu ati eto ọrọ aje Naijiria. Awọn ofin eto idibo ti yipada, ẹgbẹ oṣelu to n ṣe ijọba lọwọ ti mu alekun bai bi ti ọwọja wọn de tẹlẹ, tawọn oludibo naa si n koju ipenija ọtun paapaa lori igbeaye, aisi aabo ati ina ọba ti ko duro ire.
Báyìí ni ikọ̀ aláàbò Iru Ekùn ṣe ń mu àdínkù ba ìjínigbé àti ètò ààbò tó mẹ́hẹ nílẹ̀ Yorùbá pẹ̀lú ọmọ ẹgbẹ́ tó lé ní 80,000 - Sunday Igboho
Igboho lo sọrọ yii ninu atẹjade to fi sita lọjọ Aje, ọsẹ yii, to si ni ipa rere ni ileeṣẹ eleto aabo naa ti ko niu idagbasoke eto aabo lẹkun Iwọ Oorun.
Wo àwọn nǹkan tí Andy Burnham, Olóòtú ìjọba UK tuntun lóun yóò ṣe fún ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì
Nigba to n ṣalaye ipinnu ati erongba rẹ fun ilẹ Gẹeṣi, Burnham sọ pe bi orilẹede United Kingdom yoo ṣe duro ṣinṣin lo mumu laya oun to si jẹ oun logun julọ. Andy to jẹ Olootu keje fun UK lati 2016, sọ pe asiko ironusi bi nnkan ṣe n lọ ni U
Ìròyìn Pàtàkì
Kọ́milẹ́kọ̀ọ́
Ẹ tẹ̀lé wa lórí ìkànnì ayélujára
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Iyabo Obasanjo àti olùdíje sípò gómìnà lẹ́gbẹ́ APC l‘Ogun, Yayi, ń tutọ́ síra wọn lójú
Yayi lo n fun Iyabo Obasanjo lesi lẹyin ti Obasanjo fẹsun kan pe Yayi ko ṣe awọn nnkan to ṣeleri rẹ fun oun leyin ti oun gba pe ki wọn panupọ fẹnuko lati yan-an bi oludije sipo gomina lẹgbẹ APC.
Afurasí tíṣà tí wọ́n ló lu akẹ́kọ̀ọ́ pa jọ̀wọ́ ara rẹ̀ fún ọlọ̀pàá
Iṣẹlẹ naa waye niluu Adazi- Ani, nijọba ibilẹ Anaocha, ipinlẹ Anambra.
Àdó olóró Iran ṣekúpa ọmọ ogún Amẹ́ríkà méjì, ìkọlù bẹ̀rẹ̀ lákọ̀tun
Ileeṣẹ aabo Amẹrika, US Central Command, Centcom sọ pe awọn ọmọ ogun Amerika ṣekọlu sawọn ileeṣẹ Ologun naa, ti ileeṣẹ iroyin Iran naa si fidi rẹ mulẹ pe Amẹrika ṣekọlu si Qeshm Island to wa ni odo Strait of Hormuz.
Ìdí rèé tí ìgbéyàwó èmi àti Ayinla Kollington ṣe forí ṣánpọ́n - Salawa Abeni ṣàlàyé
Lẹyin ọdun kan o le diẹ ti Kolington to sọrọ naa ni Salawa to fi ọrọ rẹ tirẹ lede ninu ifọrrọwerọ kan pẹlu Oyinmomo TV.
Ajínigbé yọ̀ǹda òkú ìyá, dẹ́rẹ́bà àti ọ̀kan lára ọmọ ìyá mẹ́ta tí wọ́n jí gbé, bèèrè N30m
Saaju ni a ti fi to yin leti pe awọn ajinigbe gbe awọn eeyan naa lasiko ti wọn n rin irinajo lati Abuja si Okelenyi, ipinlẹ Benue lati sin oku iya wọn.
Mọ̀ nípa ìtàn ife ẹ̀yẹ àgbáyé àti òdiwọ̀n góòlù tí wọ́n fi ṣe ife ẹyẹ ọdún 2026
Akọsilẹ fi han pe o to $713,000 (£532,000)
Wo ìdí tí ECOWAS ṣe fòǹtẹ̀ lu ríri ọ̀pá gáàsì láti Nàìjíríà lọ Morocco dé Yúróòpù, àti ìpè láti kọjú oro sí South Africa lórí àtakò rẹ̀ sáwọn adúláwọ̀ míì
Aarẹ Naijiria, Bola Tinubu sọ pe ti awọn olori orilẹ ede Africa ba kọ lati dakẹ, ti wọn ko ba gbiyanju pana aawọ, o ṣeeṣe ko mu alekun ba aisi igbọra ẹni ye nilẹ Africa.
Ilé aṣòfin Amẹrika buwọ́lù àbá láti dá ìrànwọ́ Amẹrika fún Naijiria dúró títí tíjọba yóò fi wá ojútùú sí ìṣekúpani àwọn Kristẹni
Aṣofin Gregory Stuebe to n ṣoju ẹkun Florida lo da aba naa l'Ọjọru ki gbogbo ile to gba a wọle.








































































