BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ehonu
Adeleke gbẹ́sẹ̀ lé ẹgbẹ́ awakọ̀ èrò l‘Osun, pàṣẹ fún ọlọ́pàá láti ṣoro fún ẹni tó bá tàpá ṣófin
24 Agẹmo 2026
Ìwádìí BBC rèé lórí ẹ̀sùn àjẹbánu ₦44m táwọn aṣòfin Ondo fi kan Olórí ilé tí wọ́n fi ni kó fipò sílẹ̀
24 Agẹmo 2026
Ọkùnrin tó gbé aláìsàn wá sílé ìwòsàn Adeoyo n'Ibadan yarí pé kò sí dókítà lẹ́nu iṣẹ́, ó yájú sí Nọ́ọ̀sì, ẹgbẹ́ àwọn Nọ́ọ̀sì fọnmú
22 Agẹmo 2026
5:04
Fídíò,
"Bàbá mi ti fẹ́ mú ọjọ́ ìgbeyàwó mi, kí wọn tó dú u lọ́rùn sínú oko, à ṣe ẹni ẹlẹ́ni ní yóò gba ìṣe rẹ̀ ṣe"
, Duration 5,04
21 Agẹmo 2026
Iyabo Obasanjo àti olùdíje sípò gómìnà lẹ́gbẹ́ APC l‘Ogun, Yayi, ń tutọ́ síra wọn lójú
21 Agẹmo 2026
Wo bí ìwọ́de tako àwọn ọmọ ilẹ̀ òkèèrè ṣe gbérasọ lórílẹ̀èdè South Africa, àtàwọn agbègbè tí yóò ti wáyé
30 Òkùdu 2026
"Ìjọba, olùkọ́, àwọn ọmọ wa ń fi ẹsẹ̀ gbálẹ̀, tẹ̀lé Eléégun kiri, ẹ ṣí ilé ẹ̀kọ́ padà"
26 Òkùdu 2026
Báwọn ọmọ Nàíjíríà ṣe wà nínú ìbẹ̀rù àti ìpayà ní South Africa, ìṣí kejì wọn padà délé láàrin gbèkéde ìparí oṣù tí wọn fún wọn
25 Òkùdu 2026
Àlàyé lórí báwọn ọ̀dọ́ kan ṣe fi ipá mú abílékọ jáde ní àhámọ́ ọlọ́pàá tí wọ́n sì dáná sun ún
23 Òkùdu 2026
Ṣé lóòótọ́ ni Kọmíṣọ́nà ọlọ́pàá Osun ń hùwà kò kàn mí sí rògbòdìyàn òṣèlú àti ètò ààbò tó mẹ́hẹ ní ìpínlẹ̀ náà? Ohun tí a mọ̀ rèé
16 Òkùdu 2026
Saheed Osupa, gbajúmọ̀ akọrin fuji ti pariwo síta lórí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso; ohun tó sọ rèé
4 Òkùdu 2026
2:16
Fídíò,
"Ìjọba rí epo rọ̀bì ní ìlú wa àmọ́ a kò jàǹfààní kankan, kò sí omi, iná, ojú ọ̀nà, ààbò, iléẹ̀kọ́ àti ilé ìwòsàn"
, Duration 2,16
26 Èbibi 2026
Èèyàn mẹ́rin kú níbi táwọn awakọ̀ èrò tí ń ṣe ìfẹ̀hónúhàn lórí àfikún owó epo bẹntiróòlù
18 Èbibi 2026
Àlàyé rèé lórí ohun fà á táwọn òṣìṣẹ́ tó ń pèsè omi àti ètò ọ̀gbìn ṣe gunle ìyánṣẹ́lódì
11 Èbibi 2026
Àlàyé rèé lórí ohun táwọn iléeṣẹ́ ìbáraẹnisọ̀rọ̀ ṣe tí ìjọba àpapọ̀ ṣe fọnmú mọ́ wọn lọ́wọ́
11 Èbibi 2026
1:41
Fídíò,
Ìjà ìlú wa là ń gbè, a gbà, tí ẹ bá ní à ń ṣe ìwà ipá sáwọn àjèjì - Àwọn ọmọ South Africa ṣe ìwọ́de
, Duration 1,41
28 Ìgbé 2026
Kí ló fa ogun 'Wẹtiẹ' tíjọba ológun ṣe bi ìjọba alágbádá àkọ́kọ́ wó, èyí tó mú ọ̀pọ̀ ẹ̀mí lọ àti ẹ̀kọ́ tó yẹ káwọn olóṣèlú àsìkò yìí kọ́?
27 Ìgbé 2026
Wo àwọn owó àjẹmọ́nú òṣìṣẹ́ tí ìjọba àpapọ̀ ṣàfikún rẹ̀ àti ìdí tí NLC ṣe yínmú lórí àfikún náà
27 Ìgbé 2026
3:51
Fídíò,
Wọ́n kó Rasheed mérò níbi ìwọ́de EndSARS lọ́dún 2020, ọdún mẹ́fà ló lò lẹ́wọ̀n
, Duration 3,51
20 Ìgbé 2026
Dárúkọ pẹ̀lú ẹ̀rí tó dájú àwọn tó fi rìbá lọ̀ ọ́ láti gbé ìgbésẹ̀ ìyọnípọ̀ Makinde bíbẹ́ẹ̀kọ́... - Olórí ilé aṣòfin àná
15 Ìgbé 2026
3:16
Fídíò,
Kí ni ẹ̀ṣẹ̀ wa ní Ido-Ani, tí ìjọba Ondo fi pa wá tì láìsí ilé ìwòsàn àti ojú ọ̀nà tó dára? – Aráàlú fárígá
, Duration 3,16
13 Ìgbé 2026
Ìjọba Naijiria tọrọ àforíjì lẹ́yìn rògbòdìyàn tó bẹ́ sílẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ oyè jíjẹ ní South Africa
1 Ìgbé 2026
Àwọn agbébọn ṣekúpa àgbè, aráàlú faraya, ṣe ìfẹ̀hónúhàn ní Ondo
3 Ẹrẹ̀nà 2026
Tí Trump bá ṣèkọlù sí Iran, a ṣetán láti gbẹ̀san lára Amẹrika - Ìjọba Iran
11 Sẹ́rẹ́ 2026
Page
1
nínú
28
1
2
3
4
5
6
7
28
Tókàn