BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Ojú ewé to wà yìí,
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ojú ewé to wà yìí,
Fídíò
Fídíò
Ìbejì ló wù wá láti fẹ́ láti ilẹ̀, a ti wà pọ̀ fún ọdún mẹ́wàá, a fẹ́ fẹ́ àwọn ìbejì kan tẹ́lẹ̀ àmọ́ ìwà àti ẹ́jẹ́ wa kò papọ̀ - Ìbejì Oguntoye
23 Òkùdu 2026
9:37
Fídíò,
"Búrẹ́dì ni ọkọ mi lọ rà fún àkọ́bí wa, tí wọ́n fi ṣá a pa ní ọ̀sẹ̀ kan lẹ́yìn ìkómọ ọmọ wa kejì"
, Duration 9,37
23 Òkùdu 2026
2:35
Fídíò,
"Ó ṣe ni láàánú pé gómìnà tó fi ebi pa aráàlú, tí kò ṣe dáadáa, ni wọ́n tún fi màgòmágó dá padà síjọba"
, Duration 2,35
22 Òkùdu 2026
5:08
Fídíò,
Emi ni obìńrin àkọ́kọ́ tí yóò lo wáyà iná tí kò wúlò láti ṣe iṣẹ́ ọ̀nà àwòrán - Patience Adekunle
, Duration 5,08
22 Òkùdu 2026
1:46
Fídíò,
Líla ọwọ́ sí àwọn ẹbí àti ọ̀rẹ́ rẹ lè jẹ́ kí ẹ̀mí ré gùn - Ìwádìí
, Duration 1,46
18 Òkùdu 2026
3:29
Fídíò,
Ìjọba Aiyedatiwa fẹ́ lé wa kúrò ní Agọ Ireti, ó tún kọ̀ láti fún wa ní owó oṣù wa – Àwọn olùgbé Agọ Ireti
, Duration 3,29
17 Òkùdu 2026
4:55
Fídíò,
Ẹ má sá fún ọmọ ẹlẹ́gbẹ́, ẹnikẹ́ni tó bá fẹ́ wọn yóò là – Ifatolani Ayoka, Olórí emèrè ṣàlàyé
, Duration 4,55
16 Òkùdu 2026
2:38
Fídíò,
Abula: Eré ìdárayá tiwantiwa tí wọ́n fi orúkọ àmàlà, gbẹ̀gìrì àti ewédú sọ tó ti wá ń di gbajúmọ̀ káàkiri
, Duration 2,38
15 Òkùdu 2026
5:47
Fídíò,
Ademola Adeleke àti APC sọ̀kò ọ̀rọ̀ sí ara wọn lẹ́yìn ìjà òṣèlú tó wáyé l'Osun
, Duration 5,47
14 Òkùdu 2026
3:36
Fídíò,
Kola Oyewo: Ó ti tó ọdún méje ti Kola Oyewo ti ń ṣàìsàn kó tó jáde láyé - Ẹbí
, Duration 3,36
14 Òkùdu 2026
3:53
Fídíò,
Mo máa pèsè ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ fáráàlú tí mo bá di gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti – Segun Akande
, Duration 3,53
13 Òkùdu 2026
3:37
Fídíò,
'A gba ìjọba arawa, a fi ń nira wa lára' - Àwọn aráàlú sọ èrò wọn lórí ọdún mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n ìṣèjọba àwaarawa
, Duration 3,37
12 Òkùdu 2026
1:13
Fídíò,
Ìdí mẹ́rin tí nǹkan ọkùnrin ṣe máa ń nàró ní àárọ̀ tí wọn bá jí
, Duration 1,13
11 Òkùdu 2026
5:36
Fídíò,
"Àwọn agbébọn tó ń jà fún ẹ̀sìn gan ń lo òògùn ìbílẹ̀, ṣé ìjọba le fi 1000 Kùránì àti 1m Bíbélì jagun agbébọn báyìí?"
, Duration 5,36
10 Òkùdu 2026
3:47
Fídíò,
Ó pẹ́ tí mo ti sá kúrò nílé, mo rán ara mi ní fásitì, ọjọ́ kan làwọn òbí mi rí mi lórí Tẹlifísàn bíi gbajúmọ̀ akọrin - Shodey
, Duration 3,47
9 Òkùdu 2026
3:05
Fídíò,
"Ìdájọ́ ikú tí wọ́n dá fún àwọn tó kọlu ṣọ́ọ̀ṣì Owo kò dá ọmọ mi àti àbúrò mi méjì tí wọ́n pa padà"
, Duration 3,05
5 Òkùdu 2026
3:52
Fídíò,
Eku ò ké bí eku mọ́ ní Ekiti, 'èmi ló kàn' láti dá nǹkan padà bọ̀ sípò – Oluwadare Abejide, Olùdíje ADC fún ìbò gómìnà
, Duration 3,52
5 Òkùdu 2026
1:27
Fídíò,
Bí o bá ń pẹ́ kí o tó sùn lálẹ́, ewu ń bẹ fún ìlera ọpọlọ rẹ
, Duration 1,27
4 Òkùdu 2026
4:11
Fídíò,
Bàbá mi ló pàṣẹ fún mi lójú àlá pé kí n máa múra bí ọkùnrin – Funmilayo Elemure Ogunyemi
, Duration 4,11
3 Òkùdu 2026
Aṣọ kan ló kù lọ́rùn àwọn òbí mi nítorí ẹ̀kọ́ mi, ètò ẹ̀yáwókàwé NELFUND ló kó mi yọ láti kẹ́kọ̀ọ́ jáde – Oladepo Gbenga akẹ́kọ̀ọ́ tó mókè jùlọ ní fásitì LAUTECH
2 Òkùdu 2026
0:37
Fídíò,
Aráàlú fárígá, ṣèwọ́de ní Ibadan tako ìjọba lórí bí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ tí wọ́n jí gbé ṣì ṣe wà ní àhámọ́
, Duration 0,37
1 Òkùdu 2026
''Èyi ni ipa tí Bàba-bàbá mi kó nínú ogun abẹ́lé Biafra''-Meji Alabi, gbajúmọ̀ adarí orin
1 Òkùdu 2026
2:45
Fídíò,
Ìfúpá àwọn èèyàn Ayetoro l‘Ondo ń ga sí, torí bí òkun ṣe ń ya wọ ìlú, gbé iléẹ̀kọ́, ilégbèé, iléeṣẹ́, ilẹ̀ àti ibojì òkù lọ
, Duration 2,45
29 Èbibi 2026
Taa ni Balogun Kuku, bàbá olówó tó mú ẹ̀sìn Islam wọ ilẹ̀ Ijebu, tó tún bẹ̀rẹ̀ ọdún Ojude Ọba?
28 Èbibi 2026
Ìṣájú
Page
2
nínú
40
1
2
3
4
5
6
7
8
40
Tókàn