BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Orilẹede Naijiria
1:07
Orin,
Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́
, Duration 1,07
wákàtí 7 sẹ́yìn
Ọmọ Nàìjíríà míràn tún kú sọ́wọ́ ọlọ́pàá ní South Africa; Ìjọba Nàìjíríà fárígá, pè fún ìwádìí kíkún
wákàtí 8 sẹ́yìn
Àfiwé owó oṣù àwọn ṣọ́jà Nàìjíríà pẹ̀lú àwọn akẹgbẹ́ wọn lórílẹ̀èdè míràn ní Áfíríkà
27 Agẹmo 2026
5:16
Fídíò,
Àdó olóró àwọn ajínigbé pa Shuaibu aṣọ́gbóọba lásìkò tó ń lé àwọn tó jí akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ gbé ní Oriire, àwọn ẹbí rẹ̀ pariwo síta
, Duration 5,16
27 Agẹmo 2026
America kìlọ̀ fáwọn ọmọ Nàìjíríà tó tún jẹ́ ọmọ America láti má ṣe lo ìwé ìrìnná míràn yàtọ̀ sí ti orílẹ̀èdè náà láti wọlé tábì jáde l'America
27 Agẹmo 2026
Olórí àwọn tó ń pèsè owó fún ẹgbẹ agbésùnmọ̀mí ISWAP ní Naijiria jọ̀wọ́ ara rẹ̀ fún ọmọ ogun
26 Agẹmo 2026
Kókó nǹkan tó ṣẹlẹ̀ nínú ìjà àkọ́kọ́ tí Anthony Joshua jà lẹ́yìn tí ìjàmbá ọkọ̀ gbẹ̀mí àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ ní Naijiria
26 Agẹmo 2026
Fọ́nrán bí Abacha ṣe kú wà lọ́wọ́ mi, arúmọjẹ lásán ni ìtàn táwọn kan ń kọ sínú ìwé kiri - Al-Mustapha, olórí ẹ̀ṣọ́ aláàbò fún Abacha
26 Agẹmo 2026
Kókó ìpàdé Sẹ́nẹ́tọ̀ Folarin pẹ̀lú Ààrẹ Tinubu lórí awuyewuye nípa olùdíje sípò gómìnà fẹ́gbẹ́ APC ní ìpínlẹ̀ Oyo
25 Agẹmo 2026
Ọlọ́pàá mẹ́rin tó bèèrè owó ẹ̀yìn lọ́wọ́ awakọ̀ lọ́nà márosẹ̀ Ọrẹ si Benin wọ gàù, ilé-iṣẹ́ ọlọ́pàá bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí wọn
25 Agẹmo 2026
Ilé ẹjọ́ gba onídùúró Blessing CEO pẹ̀lu ₦20m lórí ẹ̀sùn jìbìtì ₦69.15m
24 Agẹmo 2026
Wo àwọn àyípadà tó máa wáyé sí ètò ààbò bí Ààrẹ Tinubu ṣe buwọ́lu àfikún ẹkùn iléeṣẹ́ ológun di méjìlá
24 Agẹmo 2026
Ilé ìgbìmọ̀ Aṣojú-ṣòfin buwọ́lu àbádòfin fún ìdásílẹ̀ ọlọ̀pàá ìpínlẹ̀ lórílẹ̀èdè Nàìjíríà
23 Agẹmo 2026
Wo ìdí tí Trump ṣe kọ lẹ́tà, kan sáárá sí Tinubu lórí gbígbógun ti ìgbéṣúmọ̀mí
23 Agẹmo 2026
1:46
Fídíò,
Ohun tí BBC rí rèé níbùdó tí wọn ti ń po kẹ́míkà pọ̀ lọ́nà àìtọ̀ tó tó $400m táwọn ọmọ ilẹ̀ Mexico ń ṣe
, Duration 1,46
23 Agẹmo 2026
ICPC ṣàwárí ayédèrú òṣìṣẹ́ 908 láwọn iléeṣẹ́ ìjọba Nàìjíríà àádọ́ta, ọlọ́pàá pọ̀ nínú wọn
23 Agẹmo 2026
Wo ohun tó ń fà àìsàn rọpárọsẹ̀, ìtọ́jú àti ìdènà rẹ̀, báwọn èèyàn ṣe ń ní àìsàn náà láàrin ìṣẹ́jú kọ̀ọ̀kan ní Naijiria
22 Agẹmo 2026
Ọlọ́pàá mẹ́rin tó gbégi dínà lójú pópó fi tipá gba rìbá N57,000 lọ́wọ́ ọ̀gá àjọ tó ń gbógun tìwà àjẹbánu, ICPC, ọ̀rọ̀ bẹ́yìn yọ
22 Agẹmo 2026
Wo àwọn nǹkan mẹ́fà tó ti yípadà lẹ́yìn ìdìbò 2023 tó le nípa lórí ìdìbò 2027
21 Agẹmo 2026
Báyìí ni ikọ̀ aláàbò Iru Ekùn ṣe ń mu àdínkù ba ìjínigbé àti ètò ààbò tó mẹ́hẹ nílẹ̀ Yorùbá pẹ̀lú ọmọ ẹgbẹ́ tó lé ní 80,000 - Sunday Igboho
21 Agẹmo 2026
Ajínigbé yọ̀ǹda òkú ìyá, dẹ́rẹ́bà àti ọ̀kan lára ọmọ ìyá mẹ́ta tí wọ́n jí gbé, bèèrè N30m
20 Agẹmo 2026
Aisha Achimugu, bọ̀rọ̀kìnní obìnrin tí iléẹjọ́ gbẹ́sẹ̀lé ẹ̀ṣọ́ ara àti ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ tí owó rẹ̀ tó ₦8.9bn lẹ́yìn tí EFCC fí ẹ̀sùn kíkọ́rọ̀ jọ lọ́nà èrú kàn án
17 Agẹmo 2026
Gbogbo ìgbà ti ọmọ mi bá rí àlejò ni ẹ̀rù máa ń bà á báyìí – Ìyá akẹ́kọ̀ọ́ tó gba ìtúsílẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Oyo
17 Agẹmo 2026
6:21
Fídíò,
Ìpinnu mi láti di gómìnà ìpínlẹ̀ Osun jẹ́ kádàrá èmi àti Ọlọ́run – Bola Oyebamiji olùdíje APC
, Duration 6,21
17 Agẹmo 2026
Page
1
nínú
40
1
2
3
4
5
6
7
40
Tókàn